FIBAN LAGOS

FIBAN LAGOS

Share

Photos from FIBAN LAGOS's post 15/12/2021

Gómìnà Sanwoolu, Lọ́jọ́ọ Mánigbàgbé Nínú Ètò Ẹ̀kọ́!

Ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejìlá ọdún 2021 nínú ètò ẹ̀kọ́ nìpínlẹ̀ Èkó jẹ́ ọjọ́ ńlá.

Gómìnà Babajídé Sanwóolú ṣí ilé ìwé ìgbàlódé Ẹlẹ́mọrọ̀ Community school ní ìjọba ìbílẹ̀ Ìbẹ̀jù Lẹ́kí.

Ilé ìwé ìgbàlódé yìí yàtọ̀ sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé ìwé ìjọba nítorí wọn kọ àwọn ǹkan wọ̀nyí kún ilé ìwé yìí:
Ilé ìwòsàn
Ilé ìkàwé
Ilé ìmọ̀ ìjìnlẹ̀
Ilé ìmọ̀ orin
Pápá ìṣeré ìgbàlódé.

Gómìnà Babajídé Sanwóolú sọ pé kíkọ irú ilé ìwé ìgbàlódé yìí wà nínú àfojúsùn THEMES Agenda.

Ẹ Gbọ́, ṣe owó gọbọi tí gómìnà ná lórí ilé Ẹ̀kọ́ yìí kò pọ̀jú fún idagbasoke eto ẹ̀kọ́?

Kí ni èrò yín?

Want your business to be the top-listed Media Company in Lagos?
Click here to claim your Sponsored Listing.

Telephone

Address


Lagos